Nigerian Defence Academy
From Wikipedia, the free encyclopedia
Nigerian Defence Academy tabi Ile-eko Oro Abo Naijiria ni yunifásítì ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fun awon omo-ologun to wa ni ilu Kaduna[1][2]. Akoko ikẹẹkọ Ile-eko Oro Abo Naijiria jẹ ọdun marun (Ọdun mẹrin fun ti akadẹmi ati ọdun kan fun ti ologun)[3].